Kí Ni Bíbélì Sọ Nípa Ìwà-bí-Ọlọ́run? — Gbígbé E Jáde Ní Ìṣe · Àwọn Ìwé Mímọ́ KJV pẹ̀lú Àwọn Nọ́mbà Strong — Ìdánwò Bíbélì
For each reference below, choose what that verse teaches. Your score appears at the end.
This is the graded quiz. Pass it to earn credit toward your Ministry Certificate of Endorsement.
2 Peteru 1:3 — Bí agbára rẹ̀ bí Ọlọ́run ti fún wa ní ohun gbogbo tí a nílò fún ṣe ti ìyè àti ti ________, nípa ìmọ̀ ẹni tí ó pè wá nípa Ògo àti ìṣeun rẹ̀.
sùúrù
ìwà-bí-Ọlọ́run
àìṣòdodo
1 Timotiu 3:16 — Láìṣiyèméjì, títóbi ní ohun ìjìnlẹ̀ ________: ẹni tí a fihàn nínú ara, tí a dá láre nínú Ẹ̀mí, ti àwọn angẹli rí, tí a wàásù rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, tí a gbàgbọ́ nínú ayé, tí a sì gbà sókè sínú ògo.
ìwà
ìràpadà
ìwà-bí-Ọlọ́run
1 Peteru 2:2 — Bí ọmọ ọwọ́ tuntun, kí ẹ máa fẹ́ wàrà ti Ẹ̀mí, èyí tí kò lẹ́tàn, kí ẹ̀yin lè máa tipasẹ̀ rẹ̀ dàgbà sí ________
iṣẹ́
ìgbàlà
ìfẹ́
Hosea 11:3 — Lóòtítọ́ mo kọ́ ________ pẹ̀lú ní ìrìn mo di wọ́n mú ní apá, ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀ pé mo ti mú wọn láradá.
Asiria
Efraimu
Samaria
Saamu 34:11 — Wá, ẹ̀yin ọmọ mi, fi ________ sí mi; èmi yóò kọ́ ọ yín ní ẹ̀rù Olúwa.
etí
ẹbọ
ìlànà
Heberu 11:6 — Ṣùgbọ́n láìsí ìgbàgbọ́ kò ṣe é ṣe láti wù ú; nítorí ẹni tí ó bá ń tọ Ọlọ́run wá kò lè ṣàì ________ pé ó ń bẹ, àti pé òun ní olùṣẹ̀san fún àwọn tí o fi ara balẹ̀ wá a.
súnmọ́
gbàgbọ́
nìkan
Ìṣe àwọn Aposteli 3:2 — Wọn sì gbé ọkùnrin kan ti ó yarọ láti inú ìyá rẹ̀ wá, tí wọ́n máa ń gbé kalẹ̀ lójoojúmọ́ ní ________ tẹmpili ti a ń pè ni Dáradára, láti máa ṣagbe lọ́wọ́ àwọn tí ń wọ inú tẹmpili lọ.
orílẹ̀-èdè
ẹnu-ọ̀nà
ayọ̀
Ìṣe àwọn Aposteli 3:8 — Ó sì ń fò sókè, ó dúró, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí rìn, ó sì bá wọn wọ inú ________ lọ, ó ń rìn, ó sì ń fò, ó sì yín Ọlọ́run.
Ejibiti
tẹmpili
Júù
Gẹnẹsisi 5:24 — ________ bá Ọlọ́run rìn; a kò sì rí i mọ́ nítorí Ọlọ́run mú un lọ.
Enoku
Abeli
Biliha
Gẹnẹsisi 6:9 — Wọ̀nyí ni ìtàn Noa. Noa ________ ni ó jẹ́ olóòótọ́ ènìyàn àti ẹni tí ó pé ní ìgbà ayé rẹ̀, ó sì fi òtítọ́ bá Ọlọ́run rìn.
ìmọ́lẹ̀
nìkan
bẹ̀rù
Gẹnẹsisi 17:1 — Ní ìgbà tí ________ di ẹni ọ̀kàndínlọ́gọ́rùn-ún ọdún, Olúwa farahàn án, ó sì wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run alágbára, máa rìn níwájú mi, kí o sì jẹ́ aláìlábùkù.
Esau
Abramu
Ṣekemu
Mika 6:8 — Ó ti fihàn ọ́, ìwọ ènìyàn, ohun tí ó dára, àti ohun tí Olúwa ń béèrè lọ́wọ́ rẹ? Bí kò ṣe láti ṣe òtítọ́, kí o sì fẹ́ràn àánú, àti kí o rìn ní ________ pẹ̀lú Ọlọ́run rẹ̀.
ìrẹ̀lẹ̀
ìkọ̀sílẹ̀
bẹ̀bẹ̀
Saamu 4:3 — Ṣùgbọ́n kí ẹ mọ̀ pé, Olúwa ti ya ẹni ________ sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀; Olúwa yóò gbọ́ nígbà tí mo bá pè é.
yọ̀
dídùn
olódodo
Kolose 1:10 — Àwa sì ń gbàdúrà yìí kí ẹ lè gbé irú ìgbé ayé tó yẹ fún Olúwa kí ẹ sì máa wu ú ní gbogbo ọ̀nà, kí ẹ sì máa so èso rere gbogbo, kí ẹ sì máa dàgbà nínú ________ Ọlọ́run
nìkan
ìmọ̀
mọ̀
Galatia 5:25 — Bí àwa bá wà ________ sípa ti Ẹ̀mí, ẹ jẹ́ kí a sì máa rìn nípa ti Ẹ̀mí.
òtítọ́
láààyè
olódodo
1 Timotiu 2:1 — Nítorí náà mo gbà yín níyànjú ṣáájú ohun gbogbo, pé kí a máa ________, kí a máa gbàdúrà, kí a máa ṣìpẹ̀, àti kí a máa dúpẹ́ nítorí gbogbo ènìyàn.
ìrẹ̀lẹ̀
ìdánwò
bẹ̀bẹ̀
1 Timotiu 6:6 — Ṣùgbọ́n ________ pẹ̀lú ìtẹ́lọ́rùn èrè ńlá ni.
ìwà-bí-Ọlọ́run
sùúrù
bẹ̀bẹ̀
Titu 2:12 — Ó ń kọ́ wa láti sẹ́ ________ àti ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ayé, kí a sì máa wà ní àìrékọjá, ní òdodo àti ní ìwà-bí-Ọlọ́run ní ayé ìsinsin yìí
ìyapa
àìwà-bí-Ọlọ́run
ìrẹ̀lẹ̀
1 Timotiu 6:11 — Ṣùgbọ́n ìwọ ènìyàn Ọlọ́run, sá fún nǹkan wọ̀nyí; kí ó sì máa lépa òdodo, ________, ìgbàgbọ́, ìfẹ́ sùúrù, ìwà tútù.
ìwà-bí-Ọlọ́run
bẹ̀bẹ̀
ìrẹ̀lẹ̀
2 Peteru 1:6 — àti àìrékọjá kún ________; àti sùúrù kún àìrékọjá; àti ìwà-bí-Ọlọ́run kún sùúrù.
mọ̀
títí
ìmọ̀
1 Timotiu 6:12 — Máa ja ìjà rere ti ìgbàgbọ́, di ìyè àìnípẹ̀kun mú nínú èyí tí a pè ọ sí, ti ìwọ sì ṣe ________ rere níwájú ẹlẹ́rìí púpọ̀.
bẹ̀bẹ̀
ìjẹ́wọ́
ìsọdọmọ
1 Timotiu 1:18 — Àṣẹ yìí ni mo pa fún ọ, ________ ọmọ mi, gẹ́gẹ́ bí ìsọtẹ́lẹ̀ wọ̀nyí tó ó ti ṣáájú nípa rẹ̀, pé nípasẹ̀ wọ́n kí ìwọ lè máa ja ìjà rere;
Timotiu
Efesu
Antioku
2 Timotiu 2:3 — Ṣe ________ pẹ̀lú mi nínú ìpọ́njú, bí ọmọ-ogun rere Jesu Kristi.
ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́
alábápín
ìkọ̀sẹ̀
2 Timotiu 2:4 — Kò sí ẹni tí ń jagun ti ń fi ohun ayé yìí dí ara rẹ̀ lọ́wọ́, kí ó lè mú inú ẹni tí ó ________ ni ọmọ-ogun dùn.
yàn
ọlá
rán
Efesu 6:11 — Ẹ gbé gbogbo ìhámọ́ra Ọlọ́run wọ̀, kí ẹ̀yin lè kọ ojú ìjà sí ________ èṣù.
ìrẹ̀lẹ̀
ìgboyà
àrékérekè
Romu 6:13 — Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹ̀yà ara yín kan di ohun èlò ohun búburú, nípa ẹ̀ṣẹ̀ dídá. Ṣùgbọ́n ẹ fi wọn fún Ọlọ́run pátápátá. Wọ́n ti di ààyè, ẹ jẹ́ kí wọn di ohun èlò ní ọwọ́ Ọlọ́run, kí ó lè lò wọ́n fún àwọn ________ rẹ̀ tí ó dára.
ìlànà
ìlérí
ìpọ́njú
2 Timotiu 3:12 — Nítòótọ́, gbogbo àwọn tí ó fẹ́ máa gbé ìgbé ayé ________ nínú Kristi Jesu yóò faradà inúnibíni.
ìwà-bí-Ọlọ́run
ìrònúpìwàdà
àìṣòdodo
1 Kọrinti 9:24 — Ẹ̀yin kò mọ̀ pé, olúkúlùkù ẹni tí ó ní ________ nínú eré ìje ni ó máa ń sáré, ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣoṣo ni ń gba ipò ẹ̀bùn tí ó ga jù. Nítorí náà, ẹ sá eré ìje yín kí ẹ ba à le borí.
ọ̀tá
àgbélébùú
ipa
1 Kọrinti 9:25 — Gbogbo ẹni tí ó ń sáré ìje a máa lọ nínú ìsẹ́ra-ẹni tí ó lágbára. Wọ́n ń ṣe èyí láti gba adé ________. Ṣùgbọ́n àwa ń sá eré ìje tiwa láti fi gba adé ọ̀run àìdíbàjẹ́ láéláé.
ìdíbàjẹ́
ìyàtọ̀
ìfihàn
Link copied
Has this study helped you? Share a short or your full testimony — your story helps someone else find this site.
Save your progress
Optional. You never need an account to use this site.
Keep your quiz scores and your certificate if you change phone or clear your browser.
Restore progress
Restoring replaces the progress on this device, and any certificate you print afterwards will carry the name on the record.
