Kí Ni Bíbélì Wí Nípa Ìfaradà? — Apá 2 · Àwọn Ìwé Mímọ́ KJV Pẹ̀lú Àwọn Nọ́mbà Strong — Ìdánwò Bíbélì
For each reference below, choose what that verse teaches. Your score appears at the end.
This is the graded quiz. Pass it to earn credit toward your Ministry Certificate of Endorsement.
Heberu 10:36 — Nítorí ẹ̀yin kò le ṣe aláìní ________, nítorí ìgbà tí ẹ̀yin bá ti ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run tan kí ẹ̀yin le gba ìlérí náà.
sùúrù
ìgboyà
pípé
Heberu 12:1 — Nítorí náà bí a ti fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ tí o kún fún àwọn ẹlẹ́rìí tó báyìí yí wa ká, ẹ jẹ́ kí a pa ohun ìdíwọ́ gbogbo tì sí apá kan, àti ẹ̀ṣẹ̀ tí o rọrùn láti di mọ́ wa, kí a sì máa fi ________ súré ìje tí a gbé ka iwájú wa
ìgboyà
ìgbàlà
sùúrù
Luku 21:19 — Nínú ìdúró ________ yín ni ẹ̀yin ó jèrè ọkàn yín.
baálẹ̀
panṣágà
ṣinṣin
Heberu 6:12 — Kí ẹ má ṣe di onílọ̀ra, ṣùgbọ́n aláfarawé àwọn tí wọn ti ipa ìgbàgbọ́ àti ________ jogún àwọn ìlérí.
sùúrù
ìgboyà
pípé
Heberu 6:15 — Bẹ́ẹ̀ náà sì ni, lẹ́yìn ìgbà tí Abrahamu fi ________ dúró, ó ri ìlérí náà gbà.
ayọ̀
gbangba
sùúrù
Romu 8:25 — Ṣùgbọ́n bí àwa bá ń retí èyí tí àwa kò rí, ǹjẹ́ àwa ń fi ________ dúró dè é.
sùúrù
ìgbàlà
ìkọlà
Jakọbu 5:7 — Nítorí náà ará, ẹ mú sùúrù títí di ìpadà wá Olúwa. Kíyèsi i, àgbẹ̀ a máa retí ________ iyebíye ti ilẹ̀, a sì mú sùúrù dè é, títí di ìgbà àkọ́rọ̀ àti àrọ̀kúrò òjò.
èso
kún
àlàáfíà
Jakọbu 5:8 — Ẹ̀yin pẹ̀lú, ẹ mú ________; ẹ fi ọkàn yín balẹ̀, nítorí ìpadà wá Olúwa kù sí dẹ̀dẹ̀.
pípé
ìdánwò
sùúrù
Jakọbu 5:11 — Sá à wò ó, àwa a máa ka àwọn tí ó fi ara dà ìyà sí ẹni ìbùkún. Ẹ̀yin ti gbọ́ ti sùúrù ________, ẹ̀yin sì rí ìgbẹ̀yìn tí Olúwa ṣe; pé Olúwa kún fún ìyọ́nú, ó sì ní àánú.
Elijah
Noa
Jobu
Romu 15:4 — Nítorí ohun gbogbo tí a kọ tẹ́lẹ̀, ni a kọ láti fi kọ́ wa pé, nípa sùúrù àti ________ ìwé mímọ́, kí àwa lè ní ìrètí.
ìfihàn
ìtùnú
ìyàtọ̀
Romu 15:5 — Kí Ọlọ́run, ẹni tí ń fún ni ní sùúrù àti ________ fún yin láti ní inú kan sí ara yín gẹ́gẹ́ bí i Jesu Kristi
ìtùnú
ìfihàn
ìyàtọ̀
Kolose 1:11 — pé kí a lè fi ipa gbogbo sọ yín di alágbára gẹ́gẹ́ bí agbára rẹ̀ àti ògo rẹ̀, kí ó lè ṣe é ṣe fún un yín láti máa tẹ̀síwájú nínú ________ àti ìpamọ́ra pẹ̀lú ayọ̀.
ìtùnú
sùúrù
àìṣòdodo
Saamu 37:7 — Ìwọ dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú Olúwa, kí o sì fi ________ dúró dè é; má ṣe ṣe ìkanra nítorí àwọn tí ń rí rere ní ọ̀nà wọn, nítorí ọkùnrin náà ti mú èrò búburú ṣẹ.
òmùgọ̀
sùúrù
ẹ̀kún
Saamu 40:1 — Mo fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ dúró de Olúwa; ó sì ________ sí mi, ó sì gbọ́ ẹkún mi.
dẹtí
láìnídìí
oore-ọ̀fẹ́
Ẹkún Jeremiah 3:26 — Ó dára kí a ní ________ fún ìgbàlà Olúwa.
ìfẹ́
asán
sùúrù
Jobu 13:15 — Bí ó tilẹ̀ pa mí, síbẹ̀ èmi ó máa ________ e, èmi ó máa tẹnumọ́ ọ̀nà mi níwájú rẹ̀.
gbẹ́kẹ̀lé
sinmi
ìhòhò
2 Tẹsalonika 3:5 — Kí Olúwa máa tọ́ ọkàn yín ṣọ́nà sí ìfẹ́ Ọlọ́run àti sínú ________ Kristi.
ìgbàlà
ìgbẹ́kẹ̀lé
sùúrù
Jakọbu 1:12 — Ìbùkún ni fún ọkùnrin tí ó fi ọkàn rán ________; nítorí nígbà tí ó bá yege, yóò gba adé ìyè, tí Olúwa ti ṣèlérí fún àwọn tí ó fẹ́ ẹ.
pípé
ìdánwò
ìtùnú
Link copied
Has this study helped you? Share a short or your full testimony — your story helps someone else find this site.
Save your progress
Optional. You never need an account to use this site.
Keep your quiz scores and your certificate if you change phone or clear your browser.
Restore progress
Restoring replaces the progress on this device, and any certificate you print afterwards will carry the name on the record.
