🌐 Language
'Olelo Hawai'iAfaan Oromoobahasa IndonesiaBelarusianBrezhonegCebuanoChamorroChichewachiShonaChongthuCiyawoDanskDeutschEestiEnglishEspañolEsperantoeʋegbeFrançaisHausaHrvatskiIgboIlocanoItalianoKikuyuKiswahiliKiyombiKreyòl AyisyenLatinaLatviešulietuviųLingálaLugandaMagyarMahasuiMāoriNederlandsNorskPohnpeianPolskiPortuguêsQach’abelRomaniRomânăSanskritSetswanaShqipsrpski jezikSuomiSvenskaTagalogTiếng ViệtTonganTwiTürkçeUyghur tiliYorùbáÍslenskaČeštinaБългарскиРусскийУкраїнськаעבריתاردوالعربيةفارسیكوردی سۆرانیअहिराणी‎नेपालीभद्रवाही‎मराठीमानक हिन्दी‎हरियाणवी‎অসমীয়াবাংলাਪੰਜਾਬੀગુજરાતીଓଡ଼ିଆ‎தமிழ்తెలుగుಕನ್ನಡമലയാളംไทยဗမာἙλληνική中文日本語한국어+ All languages
See More Jesus

Kí Ni Bíbélì Sọ Nípa Ìmọ̀? — Gbígbé E Yè · Àwọn Ìwé Mímọ́ KJV pẹ̀lú Àwọn Nọ́mbà Strong — Ìdánwò Bíbélì

For each reference below, choose what that verse teaches. Your score appears at the end.

This is the graded quiz. Pass it to earn credit toward your Ministry Certificate of Endorsement.

Òwe 1:7 — Ìbẹ̀rù Olúwa ni ìbẹ̀rẹ̀ ìmọ̀, ṣùgbọ́n aláìgbọ́n kẹ́gàn ọgbọ́n àti ________.
ẹ̀kọ́
òtítọ́
ìwà
Òwe 2:3 — àní, bí ìwọ bá ké tọ ìmọ̀ lẹ́yìn, tí ìwọ sì gbé ohùn rẹ sókè fún ________
èrè
òye
ìrètí
Òwe 2:4 — bí ìwọ bá ṣàfẹ́rí rẹ̀ bí i ________ tí ìwọ sì wa kiri bí ìṣúra tí a fi pamọ́.
fàdákà
èso
oúnjẹ
Òwe 2:5 — Nígbà náà ni ìwọ yóò bẹ̀rù Olúwa, ìwọ yóò sì rí ________ Ọlọ́run.
òye
ìfẹ́
ìmọ̀
Òwe 18:15 — Ọkàn olóye ní i gba ìmọ̀; etí ________ ní í ṣe àwárí rẹ̀.
ọlọ́gbọ́n
sọ̀rọ̀
pàṣán
Saamu 94:10 — Ẹni tí ń bá ________ wí, ṣé kò lè tọ́ ni ṣọ́nà bí? Ẹni tí ń kọ́ ènìyàn ha lè ṣàìní ìmọ̀ bí?
òkè
ẹbọ
orílẹ̀-èdè
Saamu 25:9 — Ó ṣe amọ̀nà àwọn onírẹ̀lẹ̀ ni ohun tí ó ________, ó sì kọ́ àwọn onírẹ̀lẹ̀ ní ọ̀nà rẹ̀.
ìtẹ́
dára
òróró
Hosea 6:3 — Ẹ jẹ́ kí a mọ Olúwa; ẹ jẹ́ kí a tẹ̀síwájú láti mọ̀ ọ́n. Gẹ́gẹ́ bí ________ ṣe ń yọ, yóò jáde; yóò tọ̀ wá wá bí òjò, bí òjò àkọ́rọ̀ ti ń bomirin ilẹ̀.”
ìsinmi
oòrùn
ìbùkún
Johanu 7:17 — Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀ yóò mọ̀ ní ti ________ náà, bí ìbá ṣe ti Ọlọ́run, tàbí bí èmi bá sọ ti ara mi.
apá
ẹ̀kọ́
ẹ̀ka
Matiu 11:29 — Ẹ gbé ________ mi wọ̀. Ẹ kọ́ ẹ̀kọ́ lọ́dọ̀ mi nítorí onínútútù àti onírẹ̀lẹ̀ ọkàn ni èmi, ẹ̀yin yóò sì ri ìsinmi fún ọkàn yín.
àdúrà
onírúurú
àjàgà
2 Peteru 3:18 — Ṣùgbọ́n ẹ máa dàgbà nínú ________ àti nínú ìmọ̀ Olúwa àti Olùgbàlà wa Jesu Kristi. Ẹni tí ògo wà fún nísinsin yìí àti títí láé! Àmín.
asán
ìrètí
oore-ọ̀fẹ́
2 Peteru 1:5 — Àti nítorí ìdí èyí, ẹ máa ṣe àìsimi gbogbo, ẹ fi ìwà rere kún ________, àti ìmọ̀ kún ìwà rere;
ìmọ́lẹ̀
níhìn-ín
ìgbàgbọ́
Òwe 10:14 — Ọlọ́gbọ́n ènìyàn kó ìmọ̀ jọ, ṣùgbọ́n ẹnu aláìgbọ́n a máa ṣokùnfà ________.
ìparun
níwájú
ayọ̀
Òwe 15:14 — Ọkàn olóye ń wá ìmọ̀ ṣùgbọ́n ẹnu ________ ń fẹ́ ìwà òmùgọ̀ bí ẹní jẹun.
ẹlẹ́ṣẹ̀
aláìgbọ́n
kìnnìún
Kolose 1:9 — Nítorí ìdí èyí, láti ọjọ́ tí a ti gbọ́ nípa yín, a kò sinmi láti máa gbàdúrà fún yin, tí a sì ń gbàdúrà pé kí Ọlọ́run fi ìmọ̀ ìfẹ́ rẹ̀ kún yín nípasẹ̀ ọgbọ́n àti òye gbogbo tí ń ṣe ti ________.
ìjọ
Ẹ̀mí
tọ́
Kolose 1:10 — Àwa sì ń gbàdúrà yìí kí ẹ lè gbé irú ìgbé ayé tó yẹ fún Olúwa kí ẹ sì máa wu ú ní gbogbo ọ̀nà, kí ẹ sì máa so èso rere gbogbo, kí ẹ sì máa dàgbà nínú ________ Ọlọ́run
mọ̀
ìmọ̀
ìrètí
Filipi 1:9 — Èyí sì ni ________ mi: pé kí ìfẹ́ yín lè máa pọ̀ síwájú àti síwájú sí i nínú ìfẹ́ àti ìmọ̀ ìjìnlẹ̀
àdúrà
èrò
iṣẹ́
1 Kọrinti 8:1 — Ní ìsinsin yìí, nípa tí oúnjẹ ti a fi rú ẹbọ sí ________, a mọ̀ pé gbogbo wa ni a ní ìmọ̀. Imọ̀ a máa fẹ́ mu ní gbéraga, ṣùgbọ́n ìfẹ́ ní gbé ni ró.
ẹ̀ṣẹ̀
òrìṣà
etí
Òwe 3:6 — Mọ̀ ọ́n ní gbogbo ọ̀nà rẹ òun yóò sì máa ________ ipa ọ̀nà rẹ.
kọ̀
tọ́
òdodo
Saamu 119:66 — Kọ́ mi ní ìmọ̀ àti ìdájọ́ rere, nítorí mo gbàgbọ́ nínú ________ rẹ.
ẹ̀ṣẹ̀
àṣẹ
ìránṣẹ́
Òwe 24:5 — Ọlọ́gbọ́n ènìyàn ní agbára púpọ̀, ènìyàn tí ó ní ________ sì ń ní agbára sí i.
òye
ìfẹ́
ìmọ̀
2 Kọrinti 10:4 — Nítorí ohun ________ wa kì í ṣe ti ara, ṣùgbọ́n ó lágbára nínú Ọlọ́run láti wó ibi gíga palẹ̀.
ọlá
ìjà
gbàdúrà
2 Kọrinti 10:5 — Àwa ń sọ gbogbo èrò àti gbogbo ohun gíga ti ń gbe ara rẹ̀ ga sí ìmọ̀ Ọlọ́run kalẹ̀, àwa sì ń di gbogbo èrò ní ________ wá sí ìtẹríba fún Kristi.
ìparun
ìgbèkùn
aginjù
2 Kọrinti 4:6 — Nítorí Ọlọ́run ni ẹni tí ó wí pé, “Kí ìmọ́lẹ̀ ó tan láti inú ________ jáde,” òun ní ó ti ń tan mọ́lẹ̀ lọ́kàn wa, láti fún wa ní ìmọ́lẹ̀ ìmọ̀ ògo Ọlọ́run ní ojú Jesu Kristi.
ìgbèkùn
ìgbàlà
òkùnkùn
Efesu 6:17 — Kí ẹ sì mú ________ ìgbàlà, àti idà ẹ̀mí, tí í ṣe ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.
ìpamọ́ra
àrankàn
àṣíborí
Malaki 2:7 — “Nítorí ètè àlùfáà ní òye láti máa pa ìmọ̀ mọ́, kí àwọn ènìyàn lè máa wá ìtọ́ni ni ẹnu rẹ̀: nítorí òun ni ìránṣẹ́ Olúwa àwọn ________.
orílẹ̀-èdè
ọmọ-ogun
rán
Òwe 15:2 — Ahọ́n ọlọ́gbọ́n a máa gbé ìmọ̀ jáde ṣùgbọ́n ẹnu ________ ń tú ọ̀rọ̀ ọ òmùgọ̀ jáde.
aláìgbọ́n
ẹlẹ́ṣẹ̀
kìnnìún
1 Peteru 3:15 — Ṣùgbọ́n ẹ bọ̀wọ̀ fún Kristi bí Olúwa ní ọkàn yín: kí ẹ sì múra tan nígbà gbogbo láti dá olúkúlùkù lóhùn tí ń béèrè ìrètí tí o ń bẹ nínú yín, ṣùgbọ́n pẹ̀lú ọkàn ________ àti ìbẹ̀rù.
òmùgọ̀
sùúrù
tútù
2 Timotiu 2:15 — Ṣaápọn láti fi ara rẹ̀ hàn níwájú Ọlọ́run bi ẹni tí ó yege àti òṣìṣẹ́ tí kò ní láti tijú, tí ó ń ________ ọ̀rọ̀ òtítọ́ bí ó ti yẹ.
wọ̀
gbàgbọ́
pín

← Back to the study