🌐 Language
'Olelo Hawai'iAfaan Oromoobahasa IndonesiaBelarusianBrezhonegCebuanoChamorroChichewachiShonaChongthuCiyawoDanskDeutschEestiEnglishEspañolEsperantoeʋegbeFrançaisHausaHrvatskiIgboIlocanoItalianoKikuyuKiswahiliKiyombiKreyòl AyisyenLatinaLatviešulietuviųLingálaLugandaMagyarMahasuiMāoriNederlandsNorskPohnpeianPolskiPortuguêsQach’abelRomaniRomânăSanskritSetswanaShqipsrpski jezikSuomiSvenskaTagalogTiếng ViệtTonganTwiTürkçeUyghur tiliYorùbáÍslenskaČeštinaБългарскиРусскийУкраїнськаעבריתاردوالعربيةفارسیكوردی سۆرانیअहिराणी‎नेपालीभद्रवाही‎मराठीमानक हिन्दी‎हरियाणवी‎অসমীয়াবাংলাਪੰਜਾਬੀગુજરાતીଓଡ଼ିଆ‎தமிழ்తెలుగుಕನ್ನಡമലയാളംไทยဗမာἙλληνική中文日本語한국어+ All languages
See More Jesus

Kí Ni Bíbélì Wí Nípa Ìṣọ́ra? — Apá Kejì · Àwọn Ẹsẹ Bíbélì KJV pẹ̀lú Àwọn Nọ́mbà Strong — Ìdánwò Bíbélì

For each reference below, choose what that verse teaches. Your score appears at the end.

This is the graded quiz. Pass it to earn credit toward your Ministry Certificate of Endorsement.

2 Peteru 1:10 — Nítorí náà, ará ẹ túbọ̀ máa ṣe àìsimi láti sọ ________ àti yíyàn yín di dájúdájú, nítorí bí ẹ̀yin bá ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, ẹ̀yin kì yóò ṣubú.
alẹ́
ìpè
tẹríba
2 Timotiu 2:15 — Ṣaápọn láti fi ara rẹ̀ hàn níwájú Ọlọ́run bi ẹni tí ó yege àti òṣìṣẹ́ tí kò ní láti tijú, tí ó ń ________ ọ̀rọ̀ òtítọ́ bí ó ti yẹ.
gbàgbọ́
wọ̀
pín
Efesu 4:3 — Kí ẹ sì máa làkàkà láti pa ìṣọ̀kan Ẹ̀mí mọ́ ni ìdàpọ̀ ________.
àlàáfíà
agbára
ìfẹ́
Efesu 5:15 — Nítorí náà ẹ kíyèsi láti máa rìn ní ìwà ________, kì í ṣé bí àwọn òmùgọ̀, ṣùgbọ́n bí àwọn ọlọ́gbọ́n;
pípé
tútù
líle
Òwe 10:4 — Ọwọ́ tí ó lẹ máa ń sọ ènìyàn di tálákà, ṣùgbọ́n ọwọ́ tí ó múra ṣíṣẹ́ a máa sọ ni di ________.
ìmọ̀ràn
ojúrere
ọlọ́rọ̀
Òwe 27:23 — Rí i dájú pé o mọ ipò tí àwọn agbo ________ rẹ wà bojútó àwọn agbo màlúù rẹ dáradára;
òwúrọ̀
ẹnu-ọ̀nà
àgùntàn
Heberu 6:19 — Èyí tí àwa níbi ìdákọ̀ró ọkàn fún ọkàn wa, ìrètí tí ó dájú tí ó sì dúró ṣinṣin, tí ó sì wọ inú ilé lọ lẹ́yìn aṣọ ________;
ìkélé
ìdánwò
alárinà
Romu 12:8 — Tàbí ẹni tí ó ń gbani níyànjú, sí ìgbìyànjú; ẹni tí ń fi fún ni kí ó máa fi inú kan ṣe é; ẹni tí ń ṣe olórí, kí ó máa ṣe é ní ojú méjèèjì; ẹni tí ń ṣàánú, kí ó máa fi inú ________ ṣe é.
èrò
àlùfáà
dídùn
Romu 12:11 — Ní ti iṣẹ́ ṣíṣe, ẹ má ṣe ọ̀lẹ; ẹ máa ní ìgbóná ọkàn; ẹ máa ________ Olúwa.
rìn
sìn
ṣubú
Juda 1:3 — Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi tòótọ́, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmí ní ìtara láti kọ̀wé sí i yín nípa ìgbàlà tí í ṣe ti gbogbo ènìyàn, n kò gbọdọ̀ má kọ̀wé sí yín, kí ń sì gbà yín ní ________ láti máa jà fitafita fún ìgbàgbọ́, tí a ti fi lé àwọn ènìyàn mímọ́ lọ́wọ́ ní ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo.
ìfihàn
pípé
ìyànjú
2 Peteru 1:19 — Àwa sì ní ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ọ̀rọ̀ àwọn wòlíì dunjúdunjú sí i, èyí tí ó yẹ kí ẹ kíyèsi gẹ́gẹ́ bí fìtílà tó ń mọ́lẹ̀ níbi tí òkùnkùn gbé wà, títí ilẹ̀ yóò fi mọ́, tí ________ òwúrọ̀ yóò sì yọ lọ́kàn yín.
òwe
ìràwọ̀
ìlànà
Matiu 7:8 — Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó béèrè ń rí gbà, ẹni tí ó bá sì wà kiri ń rí, ẹni bá sì ________ ni a yóò ṣi sílẹ̀ fún.
oníṣègùn
ẹ̀rún
kànkùn
Isaiah 55:6 — Ẹ wá Olúwa nígbà tí ẹ lè ________ i; ẹ pè é nígbà tí ó wà nítòsí.
títí
iṣẹ́
Saamu 105:4 — Wá Olúwa àti ________ rẹ̀; wa ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.
òkùnkùn
ipá
ẹ̀bẹ̀
Deuteronomi 4:9 — Kìkì i kí ẹ kíyèsára, kí ẹ sì ṣọ́ra a yín gidigidi kí ẹ má ba à gbàgbé àwọn ohun tí ojú yín ti rí, kí wọn má sì ṣe sá kúrò lóókan ________ yín níwọ̀n ìgbà tí ẹ sì wà láààyè. Ẹ máa fi wọ́n kọ́ àwọn ọmọ yín àti àwọn ọmọ wọn tí ń bọ̀ lẹ́yìn wọn.
àyà
ọkọ
apá
Òwe 4:23 — Ju gbogbo nǹkan tókù lọ, pa ọkàn rẹ mọ́, nítorí òun ni ________ ìyè.
bínú
èrè
orísun
Juda 1:21 — Ẹ máa pa ara yín mọ́ nínú ________ Ọlọ́run, bí ẹ̀yin ti ń retí àánú Olúwa wa Jesu Kristi tí yóò mú yín dé ìyè àìnípẹ̀kun.
àlàáfíà
agbára
ìfẹ́
Deuteronomi 6:17 — Ẹ rí i dájú pé ẹ̀ ń pa àwọn òfin Olúwa Ọlọ́run yín mọ́ àti àwọn àṣẹ àti àwọn ________ tí ó ti fún un yín.
ìlànà
ẹ̀yà
àfonífojì
Titu 3:8 — Òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ wọ̀nyí. Mo sì fẹ́ kí ó ṣe ìtẹnumọ́ rẹ̀ gidigidi, kí àwọn tí wọ́n ti gbàgbọ́ nínú Ọlọ́run le kíyèsi láti máa fi ara wọn jì fún iṣẹ́ rere. Nǹkan wọ̀nyí dára, wọ́n sì jẹ́ ________ fún gbogbo ènìyàn.
ọlọ́rọ̀
èrè
ẹ̀bùn
Isaiah 40:31 — ṣùgbọ́n àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé Olúwa yóò sọ ________ wọn di ọ̀tun. Wọn yóò fìyẹ́ fò lókè bí idì; wọn yóò sáré àárẹ̀ kò ní mú wọn, wọn yóò rìn òòyì kò ní kọ́ wọn.
ẹ̀ṣẹ̀
agbára
ìránṣẹ́

← Back to the study