Kí Ni Bíbélì Sọ Nípa Àánú? — Apá Kejì · Àwọn Ìwé Mímọ́ KJV pẹ̀lú Àwọn Nọ́mbà Strong — Ìdánwò Bíbélì
For each reference below, choose what that verse teaches. Your score appears at the end.
This is the graded quiz. Pass it to earn credit toward your Ministry Certificate of Endorsement.
Saamu 86:15 — Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, jẹ́ aláàánú àti Ọlọ́run olójúrere, Ó lọ́ra láti ________, Ó sì pọ̀ ní ìfẹ́ àti òtítọ́.
bínú
ẹ̀tàn
orin
Saamu 86:5 — Ìwọ ń ________, ìwọ sì dára, Olúwa, ìwọ sì ṣàánú fún gbogbo àwọn tí ń ké pè ọ́.
dáríjì
ègún
kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀
Nehemiah 9:17 — Wọ́n kọ̀ láti fetísílẹ̀, wọ́n sì kùnà láti rántí iṣẹ́ ìyanu tí ìwọ ṣe ní àárín wọn. Wọ́n ṣe agídí, nínú ìṣọ̀tẹ̀ wọn, wọ́n yan ________ láti padà sí oko ẹrú wọn. Ṣùgbọ́n ìwọ Ọlọ́run tí ó ń dáríjì, olóore-ọ̀fẹ́ àti aláàánú, ó lọ́ra láti bínú, ó sì pọ̀ ní ìfẹ́. Nítorí náà ìwọ kò sì kọ̀ wọ́n sílẹ̀
olórí
wáìnì
ìwé
2 Kọrinti 1:3 — Olùbùkún ni Ọlọ́run, àti Baba Jesu Kristi Olúwa wa, Baba ìyọ́nú, àti Ọlọ́run ________ gbogbo.
ìtùnú
ìgboyà
òmùgọ̀
Ẹkún Jeremiah 3:22 — Nítorí ìfẹ́ Olúwa tí ó lágbára ni àwa kò fi ṣègbé, nítorí ti ________ rẹ kì í kùnà.
ìbínú
àánú
ọ̀tún
Saamu 103:8 — Olúwa ni aláàánú àti olóore, ó lọ́ra láti ________, ó sì pọ̀ ní ìfẹ́.
igbó
bínú
ẹ̀tàn
Mika 7:19 — Òun yóò tún padà yọ́nú sí wa; òun yóò tẹ àwọn ________ wa mọ́lẹ̀, yóò sì fa gbogbo àìṣedéédéé wa sínú ibú Òkun.
ẹ̀ṣẹ̀
ọ̀tá
ogun
Deuteronomi 4:31 — Nítorí pé Olúwa Ọlọ́run yín aláàánú ni, kò ní gbàgbé tàbí pa yín ________ tàbí kó gbàgbé májẹ̀mú pẹ̀lú àwọn baba ńlá yín, èyí tí ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ nípa ìbúra.
rẹ́
gúúsù
àríwá
Mika 6:8 — Ó ti fihàn ọ́, ìwọ ènìyàn, ohun tí ó dára, àti ohun tí Olúwa ń béèrè lọ́wọ́ rẹ? Bí kò ṣe láti ṣe òtítọ́, kí o sì fẹ́ràn àánú, àti kí o rìn ní ________ pẹ̀lú Ọlọ́run rẹ̀.
ìrẹ̀lẹ̀
ìkọ̀sílẹ̀
bẹ̀bẹ̀
Hosea 6:6 — Nítorí àánú ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ; àti ìmọ̀ Ọlọ́run ju ọrẹ ẹbọ ________ lọ.
Òkun
ìsinmi
sísun
Òwe 3:3 — Má ṣe jẹ́ kí ìfẹ́ àti òtítọ́ ṣíṣe fi ọ́ ________ láéláé so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ, kọ wọ́n sí wàláà àyà rẹ.
kọ̀
dídùn
sílẹ̀
Òwe 28:13 — Ẹni tí ó bo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ kì yóò ṣe rere, ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá ________ tí ó sì kọ̀ wọ́n sílẹ̀ máa ń rí àánú gbà.
làálàá
jẹ́wọ́
Òkúta
Saamu 51:1 — Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ bí ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ àánú rẹ̀ kí o sì pa gbogbo ________ mi rẹ́.
ẹbọ
ẹ̀ṣẹ̀
iṣẹ́
Luku 18:13 — “Ṣùgbọ́n ________ òde dúró lókèèrè, kò tilẹ̀ jẹ́ gbé ojú rẹ̀ sókè ọ̀run, ṣùgbọ́n ó lu ara rẹ̀ ní oókan àyà, ó wí pé, ‘Ọlọ́run ṣàánú fún mi, èmi ẹlẹ́ṣẹ̀!’
baálé
agbowó
ìtẹ́
Heberu 4:16 — Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí a wá si ibi ìtẹ́ oore-ọ̀fẹ́ pẹ̀lú ________, kí a lè rí àánú gbà, kí a sì rí oore-ọ̀fẹ́ láti máa ran ni lọ́wọ́ ní àkókò tí ó wọ̀.
ìgboyà
gbangba
sùúrù
Joẹli 2:13 — Ẹ sì fa ọkàn yín ya, kì í sì í ṣe aṣọ yín, ẹ sì yípadà sí Olúwa Ọlọ́run yín, nítorí tí o pọ̀ ní oore-ọ̀fẹ́, ó sì kún fun àánú, ó lọ́ra láti bínú, ó sì ṣeun púpọ̀, ó sì ________ láti ṣe búburú.
gbin
Òkúta
ronúpìwàdà
Jona 4:2 — Ó sì gbàdúrà sí Olúwa, ó sì wí pé, “Èmí bẹ̀ ọ́, Olúwa, ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ ti mo sọ kọ́ ni èyí nígbà tí mo wà ní ilẹ̀ mi? Nítorí èyí ni mo ṣé sálọ sí ________ ní ìṣáájú: nítorí èmi mọ̀ pé, Ọlọ́run olóore-ọ̀fẹ́ ní ìwọ, àti aláàánú, O lọ́ra láti bínú, O sì ṣeun púpọ̀, O sì ronúpìwàdà ibi náà.
Beti-Ṣemeṣi
Tarṣiṣi
Ekroni
Saamu 145:8 — Olóore-ọ̀fẹ́ ni Olúwa àti aláàánú ó lọ́ra láti ________ ó sì ní ìfẹ́ púpọ̀.
igbó
bínú
èlò
Luku 1:72 — Láti ṣe àánú tí ó ṣèlérí fún àwọn baba wa, àti láti rántí ________ rẹ̀ mímọ́
ìbínú
ìtẹ́
májẹ̀mú
Saamu 23:6 — Nítòótọ́, ìre àti ________ ni yóò máa tọ̀ mí lẹ́yìn ní ọjọ́ ayé è mi gbogbo, èmi yóò sì máa gbé inú ilé Olúwa títí láéláé.
ẹ̀ṣẹ̀
ìbínú
àánú
Link copied
Has this study helped you? Share a short or your full testimony — your story helps someone else find this site.
Save your progress
Optional. You never need an account to use this site.
Keep your quiz scores and your certificate if you change phone or clear your browser.
Restore progress
Restoring replaces the progress on this device, and any certificate you print afterwards will carry the name on the record.
