Kí Ni Bíbélì Sọ Nípa Àánú? — Ìpìlẹ̀ · Àwọn Ẹsẹ Bíbélì KJV pẹ̀lú Àwọn Nọ́mbà Strong's — Ìdánwò Bíbélì
For each reference below, choose what that verse teaches. Your score appears at the end.
This is the graded quiz. Pass it to earn credit toward your Ministry Certificate of Endorsement.
Matiu 9:13 — Ṣùgbọ́n ẹ lọ kọ́ ohun ti èyí túmọ̀ sí: ‘Àánú ni èmi ń fẹ́, kì í ṣe ẹbọ,’ nítorí èmi kò wá láti pe àwọn ________, bí kò ṣe àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.”
bẹ̀rẹ̀
òkú
olódodo
Jakọbu 2:13 — Nítorí ẹni tí kò ṣàánú, ni a ó ṣe ìdájọ́ fún láìsí àánú; àánú ń ________ lórí ìdájọ́.
ṣògo
ọlọ́rọ̀
ìjà
Matiu 5:7 — Alábùkún fún ni àwọn aláàánú, nítorí wọn yóò rí àánú ________.
gbà
hàn
bẹ̀rẹ̀
Efesu 2:4 — Ṣùgbọ́n Ọlọ́run, ẹni tí í ṣe ________ ni àánú, nítorí ìfẹ́ ńlá rẹ̀ tí ó fi fẹ́ wa
rara
ọlọ́rọ̀
wákàtí
1 Peteru 1:3 — Ìyìn yẹ Ọlọ́run àti Baba Jesu Kristi Olúwa wa! Ẹni tí ó tún wa bí gẹ́gẹ́ bí àánú ńlá rẹ̀ sínú ìrètí ààyè nípa ________ Jesu Kristi kúrò nínú òkú
àjíǹde
ìdánwò
ìdíbàjẹ́
Heberu 2:17 — Nítorí náà, ó yẹ pé nínú ohun gbogbo kí ó dàbí àwọn ará rẹ̀, kí ó lè jẹ́ aláàánú àti olóòtítọ́ alábojútó Àlùfáà nínú ohun tí i ṣe ti Ọlọ́run, kí o lè ṣe ________ fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn.
tútù
òmùgọ̀
ètùtù
Marku 10:47 — Nígbà tí Bartimeu gbọ́ pé Jesu ti ________ wà nítòsí, o bẹ̀rẹ̀ sí kígbe lóhùn rara pé, “Jesu ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi.”
Judea
Nasareti
Sidoni
Luku 11:41 — Nípa ohun ti inú yin, ki ẹ̀yin kúkú máa ṣe ìtọrẹ ________ nínú ohun tí ẹ̀yin ní, sì kíyèsi i, ohun gbogbo ni ó di mímọ́ fún yín.
ìránṣẹ́
ohùn
àánú
Ìṣe àwọn Aposteli 9:36 — Ọmọ-ẹ̀yìn kan sí wà ní ________ ti a ń pè ni Tabita (èyí tí ó túmọ̀ sí Dọkasi); obìnrin yìí pọ̀ ni iṣẹ́ oore, àti ìtọrẹ àánú ṣíṣe.
Nasareti
Joppa
Anderu
Gẹnẹsisi 19:19 — Nígbà tí ìránṣẹ́ rẹ ti rí ________ rẹ, tí o sì ti fi àánú rẹ hàn nípa gbígba ẹ̀mí mi là, èmi kò le è sálọ sórí òkè, kí búburú yìí má ba à lé mi bá, kí n sì kú.
ojúrere
sọkún
ìyàn
Gẹnẹsisi 19:29 — Ọlọ́run sì rántí Abrahamu, nígbà tí ó run ìlú pẹ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀n-ọn-nì tan, ó sì mú Lọti jáde kúrò láàrín ________ náà, tí ó kọlu ìlú tí Lọti ti gbé.
ìparun
ìgbàlà
ètùtù
Gẹnẹsisi 32:12 — Ṣùgbọ́n ìwọ ti ṣèlérí pé, ‘Èmi yóò mú ọ ________, èmi yóò sì mú kí àwọn ìran rẹ dà bì í yanrìn òkun tí ẹnikẹ́ni kò le è kà.’”
jogún
irọ́
gbilẹ̀
Saamu 136:1 — Ẹ fi ________ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
kọrin
ẹlẹ́ṣẹ̀
ọpẹ́
Saamu 136:4 — Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá; nítorí tí ________ rẹ̀ dúró láéláé.
ẹ̀ṣẹ̀
ìránṣẹ́
àánú
Saamu 136:23 — Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ________ wa; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
ìrẹ̀lẹ̀
ìdíbàjẹ́
òfúrufú
Saamu 136:26 — Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ________; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
ẹ̀ṣẹ̀
òtítọ́
ọ̀run
Link copied
Has this study helped you? Share a short or your full testimony — your story helps someone else find this site.
Save your progress
Optional. You never need an account to use this site.
Keep your quiz scores and your certificate if you change phone or clear your browser.
Restore progress
Restoring replaces the progress on this device, and any certificate you print afterwards will carry the name on the record.
